Ẹ Káàbọ̀!
Lítíréṣọ̀ Yorùbá is a bilingual literature website and resource hub focused on Yoruba texts, themes, and writers. À ń pèsè àyíká amáyédẹrùn fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́, olùkọ́, onímọ̀, àti gbogbo olólùfẹ́ lítíréṣọ̀ Yorùbá tí wọ́n fẹ́ kọ́ ẹ̀kọ́, ṣàwárí, tàbí kó ìmọ̀ jọ lórí ìwé Yorùbá, àwọn ònkọ̀wé Yorùbá, àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀ lọ.
Lítíréṣọ̀ Yorùbá is a digital repository of Yoruba literature in its diverse forms.
Our mission is to document and make accessible over 1,000 Yoruba literary works, spanning prose, poetry, drama, children’s books, and oral narratives.

Our scope goes beyond the texts themselves.
A gbàgbọ́ pé lítíréṣọ̀ kì í ṣe ìwé pẹ̀lú ọ̀rọ̀ nìkan. Ìdí nìyí tí a tún fi ń pèsè àkótán ìtàn, ìtúpalẹ̀ ìtàn, àfihàn ẹ̀dá ìtàn, àwọn àkòrí ìtàn, àtẹ̀jáde ìtàn àwọn ònkọ̀wé, àti ìmọ̀ èdè Yorùbá gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe farahàn nínú lítíréṣọ̀.
Events, Competitions & Literary Movements
We spotlight literary competitions, author interviews, panel discussions, book launches, and grassroots storytelling projects in the Yorùbá literary space.
Why We Created Lítíréṣọ̀ Yorùbá
Lítíréṣọ̀ Yorùbá was brought to existence to make up for the almost inexistence of Yoruba literature on the webspace. The initiators of this project recognised the need for a novel idea that will project and amplify Yoruba literature for global visibility. It is a project midwifed by several phone calls, social media chats, and meticuluous collaborations of like-minded individuals
À ń ṣe àtẹ̀jáde ìtàn àwọn onkọ̀wé Yorùbá àti ipa tí wọ́n ti kó.
À ń pèsè ìtúpalẹ̀, àkótán, àfihàn àkóónú, àti ìrànwọ́ àkànṣe fún ìdánwò bí i WAEC, NECO, àti JAMB.
À ń ṣe àkójọpọ̀ àwọn ìwe lítíréṣọ̀ Yorùbá tó tó ẹgbẹ̀rún kan (1,000).
Latest Additions
-
Àlọ́ Àpagbè láti ọwọ́ọ Adébísí Àmọ̀ó
Overview Àlọ́ Àpagbè is a collection of folktales, as its title suggests. It was written by Adébísí Àmọ̀ó in 1978 and…
-
Ọlọ́runṣògo láti ọwọ́ọ Sunday Ẹ̀ṣọ́-Olúbọ́rọ̀dé
Ọlọ́runṣògo is a novel that follows the stories of Rónkẹ́ and Fẹ́mi, who began their romantic relationship back in grammar school.
-
Ṣaworoidẹ láti ọwọ́ọ Akínwùmí Ìṣọ̀lá
Ṣaworoidẹ by Akínwùmí Ìṣọ̀lá is a politically charged allegorical narrative set in the fictional Yoruba town of Jogbo.
-
Àwọn Oríkì Orílẹ̀ Mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n láti ọwọ́ọ Adébóyè Babalọlá
Àwọn Oríkì Orílẹ̀ Mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n by Adeboye Babalola is a collection of 27 lineage praise poems of Yoruba people.
-
Àìmàsìkò àti àwọn Àròfọ̀ Mìíràn láti ọwọ́ọ Ògúnsànyà Adéṣínà
Àìmàsìkò àti àwọn Àròfọ̀ Mìíràn by Ogunsanya Adesina is a collection of thirty poems. The poems in this book are diverse.
-
Iyán Ogún Ọdún láti ọwọ́ọ Oyèwọlé Ògúnwálé
Iyán Ogún Ọdún is a Yoruba play set in the town of Ọ̀ṣun where the respected chieftaincy title of Balógun is left vacant.
Want New Updates ?
Fi àdírẹ́ẹ̀sì méèlì rẹ sílẹ̀ kí o lè gba àtẹ̀jíṣẹ́ ní gbogbo ìgbà tí a bá gbé àtẹ̀jáde tuntun jáde lórí i Lítírésọ̀ Yorùbá.






